BBC News,
Yorùbá
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀
Ìròyìn
Wò
Gbọ́
Àwọn abala
Ìròyìn
Idibo Naijiria 2027
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Idibo Naijiria 2027
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Ojude Ọba 2019: Àwọn èèkàn lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà ti péjú fún ayẹyẹ ojúde Ọba
Àkọlé àwòrán,
Ojude Oba tí ọdún yìí ti gbéra sọ pẹ̀lú oníruuru àwọn aṣọ alárànbara yorùba to ń wúni lóri, Awọn ẹgbẹ́ Tobalàṣẹ obinrin rèé nínú àṣọ okè aláwọ̀ ewé
Published
13 Ògún 2019
'Kò sí ohun tó burú nínú bí Ajimobi ṣe dá Yewande tó pa ọkọ rẹ̀ sílẹ̀'
Àwọn Fadá mẹ́rin gbà itusílẹ̀ lọwọ àwọn ajínigbé
Samuel Okwaraji: Ó pé ọgbọ̀n ọdún tí lónìí ti akọni àgbábọ̀ọ̀lù papo dà
Ẹ ṣe àwárí ọdànran tó bọ mọ́ọ yín lọ́wọ́ - Turkur Buratai
Àkọlé àwòrán,
Gbogbo àwọn ọmọ ẹgbẹ́ Gbobaniyi lókùnrin àti lóbìrin ló ti lọ ki ọba aláde lóri ìjòkò
Àkọlé àwòrán,
Lẹ́gbẹ́ lẹ́gbẹ́ ni gbogbo àwọn ti wọ́n péju síbi ayéyé Ojude Oba tí ọdún 2019
Àkọlé àwòrán,
Tokùnrin tobinrin ló wọsọ ìgbà níbi àyẹyẹ ojude oba tọdún yìí, Ẹgbẹ́ Bọbakẹ́yẹ Ọkunrin ni àwọn yìí
Àkọlé àwòrán,
Tarúgbó tomidàn ló wà nibi àyẹyẹ yìí, gbogbo oju wọ́n lo gúrégé pèlú, àwọn ẹgbẹ́ bọ́bakẹ́yẹ obinrin rèé
Àkọlé àwòrán,
Gbogbo àwọn olóyè àti èèkàn ìlú ló péjú
Àkọlé àwòrán,
Kìí ṣe àwọn ẹgbẹ́ gbẹ́ jọdá nìkàn ló péju, àwọn ọdọ náà jáde wá láti yẹ́ àṣ]a ìbílẹ̀ sí
Àkọlé àwòrán,
Aláàfin Ọyọ, ikú bábá yèyé, Ọba Lamidi Adeyemi náà péjú síbi ayẹyẹ ojúde Oba ní'lú Ijebu
Àkọlé àwòrán,
Gómínà ìpínlẹ̀ Ogun, Dapo Abiodun àti Awùjalẹ̀ Ijẹ̀bú Ọba Sikiru Adetona
Àkọlé àwòrán,
Gómìnà tẹ́lẹ̀rí ní ìpínlẹ̀ Ogun, Ọtunba Gbẹnga Daniels
Àkọlé àwòrán,
Ẹgbẹ́ Bọ́baguntẹ ilẹ̀ Ijẹbu
Àkọlé àwòrán,
Gbogbo ojú tó ti ríra típẹ tún ni àànfàni láti ṣe "Ẹ k;u àti"
Àkọlé àwòrán,
Ẹgbẹ́ Obafunwaji Obinrin Adedoyin rèé nínú aṣọ ofi aláwọ̀ búlù
Àkọlé àwòrán,
Ẹgbẹ́ Tobalaṣẹ Ọkunrin náà ko gbẹ́yìn
Àkọlé àwòrán,
Gbogbo àwọn ọmọ ẹgbẹ́ Gbobaniyi lókùnrin àti lóbìrin ló ti lọ ki ọba aláde lóri ìjòkò
Skip Móríwú and continue reading
Móríwú
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ
01:23
Fídíò,
Ìdí tí wíwọ ṣòkòtò àwọ̀tẹ́lẹ̀ péńpé 'boxer' sún kò fi dára tó fún ọ
, Duration1,23
05:31
Fídíò,
Ìbọn tí wọ́n yìn sí ọkọ mi kò ràn án, ìgbà tí wọ́n gba àpò ọwọ́ rẹ̀ ni ìbọn tó ràn án – ìyàwó ọmọ ẹgbẹ́ Accord tí wọ́n pa l'Esa Oke ṣalàyé
, Duration5,31
04:07
Fídíò,
Ìkà kọ́ lọmọ ejò, àwa èèyàn là ń kó tiwa bá wọn- Taiwo Okikiola-Ọmọ elejo
, Duration4,07
00:51
Fídíò,
Àǹfààní márùn-ún tó wà nínú kí obìnrin sùn láì wọ pátá
, Duration0,51
03:45
Fídíò,
N kò le fẹ́ ọkùnrin tó lówó, n kò sì le bá ọkùnrin jìyà tàbí ṣe ìyàwó kejì àbí ìkẹta - Eyiyemi Afolayan
, Duration3,45
05:08
Fídíò,
Emi ni obìńrin àkọ́kọ́ tí yóò lo wáyà iná tí kò wúlò láti ṣe iṣẹ́ ọ̀nà àwòrán - Patience Adekunle
, Duration5,08
02:35
Fídíò,
"Ó ṣe ni láàánú pé gómìnà tó fi ebi pa aráàlú, tí kò ṣe dáadáa, ni wọ́n tún fi màgòmágó dá padà síjọba"
, Duration2,35
01:46
Fídíò,
Líla ọwọ́ sí àwọn ẹbí àti ọ̀rẹ́ rẹ lè jẹ́ kí ẹ̀mí ré gùn - Ìwádìí
, Duration1,46
03:29
Fídíò,
Ìjọba Aiyedatiwa fẹ́ lé wa kúrò ní Agọ Ireti, ó tún kọ̀ láti fún wa ní owó oṣù wa – Àwọn olùgbé Agọ Ireti
, Duration3,29
02:38
Fídíò,
Abula: Eré ìdárayá tiwantiwa tí wọ́n fi orúkọ àmàlà, gbẹ̀gìrì àti ewédú sọ tó ti wá ń di gbajúmọ̀ káàkiri
, Duration2,38
04:55
Fídíò,
Ẹ má sá fún ọmọ ẹlẹ́gbẹ́, ẹnikẹ́ni tó bá fẹ́ wọn yóò là – Ifatolani Ayoka, Olórí emèrè ṣàlàyé
, Duration4,55
05:47
Fídíò,
Ademola Adeleke àti APC sọ̀kò ọ̀rọ̀ sí ara wọn lẹ́yìn ìjà òṣèlú tó wáyé l'Osun
, Duration5,47
01:13
Fídíò,
Ìdí mẹ́rin tí nǹkan ọkùnrin ṣe máa ń nàró ní àárọ̀ tí wọn bá jí
, Duration1,13
End of Móríwú
Ìròyìn tó ṣe kókó
Ìjọba Kwara pé Bukola Saraki lẹ́jọ́, wọ́n ló ní Gómìnà Abdulraman kò kàwé délé ẹ̀kọ́ girama
ìṣẹ́jú 54 sẹ́yìn
Ilé ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn wọ́gilé ìdájọ́ tó gba àwọn akẹ́kọ̀ọ́bìnrin láàyè láti máa wọ hijab lọ ilé ẹ̀kọ́
3 Agẹmo 2026
Ìjọba àti ẹgbẹ́ NUT ìpínlẹ̀ Oyo rọ àwọn olùkọ́ àti akẹ́kọ̀ọ́ kí wọ́n padà sílé ẹ̀kọ́
3 Agẹmo 2026
Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn
Kò sí ohun tó burú kí èèyàn máa ta àkàrà, àgbado sísun tàbí kúlíkúlí – Agbẹnusọ Ààrẹ
29 Òkùdu 2026
Ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa ikọ̀ ọlọ́pàá kògbérèégbè 'Operation Kosaye' tó gbérasọ ní ìpínlẹ̀ Eko àti Ogun
29 Òkùdu 2026
Àlàyé lórí agbègbè 200 tó léwu láti rìn sí ṣáájú ìbò gómìná ìpínlẹ̀ Osun tó ń bọ̀, INEC kéde
29 Òkùdu 2026
Sunday Igboho ṣàlàyé ipò tí òun àtàwọn ẹ̀ṣọ́ Iru Ẹkun tó farapa nínú ìkọlù Old Oyo National Park wà
29 Òkùdu 2026
Wo ohun tí òfin nọ́mbà ìdánimọ̀ tí Aarẹ ṣẹ̀ṣẹ̀ buwọ́lù túmọ̀ sí fún ọ
28 Òkùdu 2026
'Èèwọ̀ ni, n kò gbọdọ̀ f'ojú kan ìyá mi láàyè tàbí ní okú'
28 Òkùdu 2026
Mi ò kí ń ṣe aláìmoore bíi Aregbesola, mo máa ṣàtìlẹ́yìn fún Tinubu fún sáà kejì – Igboho
28 Òkùdu 2026
A máa tó gba ọkọ̀ òfurufú láti dá ààbò bo ìpínlẹ̀ Oyo, a tún máa ṣí àwọn ilé ẹ̀kọ́ padà láìpẹ́ - Makinde
28 Òkùdu 2026
Àwọn agbébọn ló dojú ààbò ilẹ̀ Yorùbá délẹ̀, digbí là wá lẹ́yìn Sunday Igboho - Afenifere
26 Òkùdu 2026
Ìròyìn tí àwọn ènìyàn fẹ́ràn jùlọ
1
Amẹ́ríkà kó àwọn ọmọ ogun rẹ̀ kúrò ní Nàíjíríà, ohun tó fàá rèé
2
Ilé ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn wọ́gilé ìdájọ́ tó gba àwọn akẹ́kọ̀ọ́bìnrin láàyè láti máa wọ hijab lọ ilé ẹ̀kọ́
3
Olùṣọ́ Àgùntàn ìjọ CCC ṣàlàyé ìdí tó fi ń ki orí àwọn ọmọ ìjọ sí ábẹ́ aṣọ
4
Ooni Ile Ife fi oyè àti ọkọ̀ tuntun dá Baba Ijesha lọ́lá
5
Ìjọba àti ẹgbẹ́ NUT ìpínlẹ̀ Oyo rọ àwọn olùkọ́ àti akẹ́kọ̀ọ́ kí wọ́n padà sílé ẹ̀kọ́
6
Wo ohun tí yóò ṣẹlẹ̀ sí owó ò rẹ tí CBN bá gbẹ́sẹ̀lé ilé ìfowópamọ́ tí ò ń lò, pẹ̀lú bí o ṣe lè rí owó rẹ̀ gbà padà
7
Mo ṣetán láti kojú ìgbẹ́jọ́ láti ṣe àfọ̀mọ́ orúkọ mi - Adeniyi Adeyemi tí ìjọba fẹ̀sùn kàn pé ó ṣe ayédèrú ìwé ìyànsípò rẹ̀
8
'Àwọn dókítà yọ kíndìnrín mi lásìkò iṣẹ́ abẹ ìbímọ'
9
Iná ṣẹ́yọ nínú ọjà Bode n'Ibadan, jó ọ̀pọ̀lọpọ̀ dúkìá
10
Ìjọba Kwara pé Bukola Saraki lẹ́jọ́, wọ́n ló ní Gómìnà Abdulraman kò kàwé délé ẹ̀kọ́ girama
More:
News
•
Sport
•
Weather
•
Worklife
•
Travel
•
Future
•
Culture
•
World
•
Business
•
Technology
•
Science_and_environment
•
Entertainment_and_arts
✕