BBC News, Yorùbá - Ìròyìn
Ìròyìn tó ṣe kókó
"Bí kò ṣe sẹ́ni tó lè fọwọ́ bo ògo òòrùn ni wọ́n kò lè dí ADC lọna"- Aregbesola fèsì bí kóòtù ṣe sún ìgbẹ́jọ́ síwájú
Aregbesola sọ eyi nibi ipade apapọ ẹgbẹ naa ti wọn n ṣe lai wo ti gbogbo ipenija to n koju wọn.
Àwọn ọmọ Iran kọminú lórí bóyá ogun Amẹ́ríkà lè tẹ̀síwájú tàbí bẹ́ẹ̀ kọ́ lẹ́yìn tí ìpàdé àláfíà forí ṣánpọ́n
Ibaṣepọ ti ko dan mọran to wa laarin Iran ati Amẹrika tunbọ buru siwaju si lẹyin ti ipade alaafia laarin orilẹede mejeji to waye ni Pakistan lulẹ.
Orin, Kò ṣe é má gbọ̀ ọ́, Duration 0,56
Kò ṣeé má gbọ̀ọ́
Amẹ́ríkà gbégi dínà Strait of Hormuz láti dí Iran lọ́wọ́ gbígbé epo gba ibẹ̀, China figbe ta pé ewu ń bẹ̀, bí owó epo ṣe wọ́n sí ní àgbáyé
Ijọba ilẹ Iran daba wiwọgile ipese Uranium fun ọdun marun un lati fopin si ogun to lọ lọwọ naa.
'Òkú mẹ́rìndínlọ́gọ́ta ni mo kà láàárín ìlú, ọ̀pọ̀ ló fọ́nká sínú igbó'
Bí àdó ikú látọ̀dọ̀ àwọn ológun Nàíjíríà tún ṣe balẹ̀ sórí aráàlu ní ọjà kan tó wà láàrin ààlà ilẹ̀ ìpínlẹ̀ Borno àti Yobe, BBC News Yoruba se akojọpọ awọn akoko mẹfa ti baalu ologun ti seesi kọlu araalu.
Fídíò, Ẹni tó bá ní kò sí ayé, ayé wà o, ohun tó jẹ mọ́ ọ̀rọ̀ ẹ̀mí wà nínú iṣẹ́ tíátà - Tosin Olaniyan, Duration 2,33
BBC News Yoruba fọ̀rọ̀ Oluwatosin Olaniyan, tí àwọn èèyàn tún ń pè ní ‘Ìdààmú Tíátà’ lẹ́nu wò, ó sọ̀rọ̀ nípa ìgbé ayé rẹ̀, eré tíátà, ọ̀rọ̀ ìfẹ́ àtawọn ohun míràn.
Ìdí rèé tí Iyabo Obasanjo ṣe gba kámú bí gbogbo ẹgbẹ́ APC l‘Ogun ṣe fa Yayi kalẹ̀ bíi olùdíje gómìnà
Ọjọ Aje, ọjọ kẹtala, oṣu Kẹrin ọdun 2026 ni Abiodun fa Yayi kalẹ, lasiko ipade awọn alẹnulọrọ ẹgbẹ APC nipinlẹ Ogun.
Ọkọ̀ tó kó àwọn agbábọ́ọ̀lù pàdé àwọn adigunjalè lọ́nà, wọ́n yìnbọn pa agbábọ́ọ̀lù kan
Ikọ agbabọọlu Berkum Chelsea ti Dominic wa lo ko awọn adigunjale lọna lọjọ Aiku ọsẹ yii.
Ìjọba gbẹ́sẹ̀ lé dúkìá afurasí mẹ́tàlá tó ń ṣagbátẹrù ìgbésùnmọ̀mí
Igbesẹ yii gẹgẹ bi ajọ SEC ṣe ṣalaye da lori ofin ọdun 2022 to tako igbesunmọmi eyi to sọ pe ijọba gbọdọ gbẹsẹ le owo, dukia ati nnkan ọrọ aje ẹnikẹni to ba n ṣagbatẹru fun igbesunmọmi lai sọ fun wọn tẹlẹ.
Àwọn ìdí rèé tí gómìnà kan fi le yọ ọba nípò lábẹ́ òfin
BBC News Yorùbá kàn sí onímọ̀ nípa òfin láti mọ̀ nípa ohun tó le ṣokùnfà kí ìjọba fi àṣẹ gba adé lórí ọba àti ìlẹ̀kẹ̀ lọ́rùn rẹ̀.
Trump kéde ìgbésẹ̀ tó kàn lẹ́yìn tí ìjíròrò pẹ̀lú Iran forí sánpọ́n
Trump, nínú àtẹ̀jáde tó fi sórí ìkànnì Truth Social rẹ̀ sọ pé ìjọba máa fi àwọn ológun ojú omi di Iran pa.
Wo ìpínlẹ̀ méje tí yóò wà nínú òkùnkùn birimù fún ọ̀sẹ̀ mẹ́fà
NISO kede wi pe lati ọjọ kẹsan an oṣu Kẹrin yii ni atunṣe yii ti bẹrẹ, yoo si pari ni ọjọ kejilelogun oṣu Karun un ọdun 2026 yii.
Móríwú
BBC News Yorùbá ti wà lórí ìkànnì WhatsApp
Má jẹ́ kí etí rẹ ó di sí gbogbo ìròyìn ohun tó ń lọ ní Naijiria àti káàkiri àgbáyé. Mọ̀ nípa wọn lórí ìkànnì Whatsapp rẹ
Ìròyìn Àkàgbádùn
Àwọn agbébọn tún ya bo ìjọba ìbílẹ̀ Kaiama ní Kwara, ṣekúpa ẹ̀ṣọ́ asọ́gbó márùn ún, dáná sun ọkọ̀ àti alùpùpù
Eyi ko ṣẹyin bi awọn agbebọn ṣe kọlu ilu naa ni nnkan bii aago mẹta owurọ oni, ọjọ kẹwaa, oṣu Kẹrin, ọdun 2026 ti wọn si ṣekupa awọn ẹṣọ asọgbo marun-un.
Fídíò, Arọ́bafin ni Sẹ́nétọ̀ Adeseun ni mo fi ní kó gáfárà fún ipò Mayegun ìlú Ogbomoso – Soun Ghandi Laoye, Duration 3,55
Ọbalaye naa ni Sẹnetọ Adeṣeun ko fi arinfin rẹ fun Ṣọun bo rara, koda o tun sọrọ alufansa sii ni gbangba.
Àwọn agbẹ́bọn tún pa ọ̀dọ́ l'Ondo, aráàlú fi ẹ̀hónú hàn
Lati le fopin si ikọlu ati ijinigbe tó n waye lemọlemọ naa, ati lati kesi ijọba fun ojutuu lo jẹ kawọn olugbe agbegbe yii gbegi di opopona to lọ si ofiisi Gomina, niluu Akure, lati fi ehonu han.
Ìjọba yóò máa gba ìwé ìrìnnà lọ́wọ́ àwọn tó bá ní àwọn kì í ṣe ọmọ Naijiria mọ́
Atẹjade naa ṣalaye pe awọn eeyan ti Aarẹ ba ti gba pe awọn ki i ṣe ọmọ Naijiria mọ ni ọrọ yii kan.
Ààrẹ Omar Guelleh tún wọlé sáà kẹfà ní Djibouti, lẹ́yìn ọdún 27 tó ti wà nípò
Ọpọ awọn to yẹ ki wọn jọ dupo aarẹ naa ni ko ba wọn kopa, awijare wọn si ni pe ko si akoyawo ninu idibo orilẹede naa mọ.
Àwọn afurasí jàndùkú agbébọn ṣekúpa ìyá àti ọmọ l'Ondo
Iṣẹlẹ yii lo tun ti fa ibẹru bojo bayii ni agbegbe naa, bi awọn eniyan se n sa asala fun ẹmi wọn, ti wọn si n kọminu lori ipo ti ọrọ eto aabo wa ni Ipinlẹ Ondo.
Agbéṣùmọ̀mí kọ lẹ́tà sáwọn èèyàn ìpínlẹ̀ Katsina, bèèrè màlúù 700, àgùtàn 1,000
Ibeere yii lo wa ninu lẹta kan ti awọn agbesunmọmi naa fi ṣọwọ si awọn ilu ti ọrọ naa kan lọjọ kẹfa, oṣu Kẹrin, ọdun 2026 ti a wa yii.
Ìdílé oyè fún Gómìnà Adeleke ní gbèdéke ọjọ́ méje láti rọ Apetumodu tó ń ṣẹ̀wọ̀n l'Ámẹ́ríkà lóyè
Ile ẹjọ kan lorilẹede Amẹrika lo dajọ ẹwọn fun Ọba Apetumodu ti ilu Ipetumodu ti wọn ni o jẹbi ẹsun lilu jibiti pẹlu eto ẹyawo COVID-19 ti wọn gbe kalẹ lati ṣe iranwọ fun awọn okoowo kekeke to fara kaasa lasiko ajakalẹ arun naa.
Ìjọba àpapọ̀ ké gbàjarè lẹ́yìn tí àrùn tó ń gbẹ̀mí màlúù kọlu ìpínlẹ̀ 17
Ijọba ni arun naa n ṣakoba fun ọrọ aje ohun ọsin ati pe ti ijọba ko ba tete kapa rẹ, o le pa odidi agbo maluu kan run.
Ta ni ọ̀gágun Braimah táwọn agbésùnmọ̀mí ṣekúpa pẹ̀láwọn ọmọogun míràn ní Borno, Tinubu kẹ́dùn pẹ̀lú ẹbí àwọn tó ṣubú lójú ìjà?
Ohun ti a gbọ ni pe lojiji lawọn agbesunmọmi naa ya wọ ibudo awọn ọmogun naa ti wọn si bẹrẹ si ni yinbọn.
Wo bí o ṣe lè wo, tàbí ṣe àtẹ̀jáde ìwé atọ́nà pélébé fún ìdánwò Jamb UTME
Ajọ Jamb ni idanwonaa yoo ṣi waye laarin ọjọ kẹrindinlogun si ikarundinlọgbọn oṣu kẹrin ọdun 2025 ti wọn kede tẹlẹ.
Ìròyìn Pàtàkì
Kọ́milẹ́kọ̀ọ́
Ẹ tẹ̀lé wa lórí ìkànnì ayélujára
Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn
Ẹ múra o! Òjò ńlá tó le fa àgbárá òjò ń bọ̀ ní ìpínlẹ̀ mẹ́wàá - NiMet
Ninu atẹjade ti ajọ naa fi sita lọjọru ni wọn ti tun sọ pe iji yoo waye lawọn ipinlẹ kan nigba ti oorun yoo si jade lawọn ibomiran.
Amẹ́ríkà gbé ìkìlọ̀ tuntun jáde lórí ọ̀rọ̀ àbò ní Nàìjíríà, Ó ní ìlú Abuja àtàwọn ìpínlẹ̀ 23 kan ti di ibi àìgbọdọ̀ wọ̀ fáwọn èèyàn rẹ̀, ìdí rèé
Ni irọlẹ Ọjọru ọjọ kẹjọ oṣu Kẹrin ọdun yii ni ileeṣẹ ijọba Amẹrika to n ri si ọrọ ilẹ okeere fi ikilọ naa sita.
Akẹ́kọ̀ọ́ Covenant University jáde láyé níbi tó ti ń gbá bọ́ọ̀lù, Ilé ẹ̀kọ́ ṣàlàyé ohun tó fa ikú rẹ̀
Ìròyìn tó gba orí ayélujára ni pé lásìkò tí akẹ́kọ̀ọ́ náà ń kópa nínú bọ́ọ̀lù àfẹsẹ̀gbá ló déédé ṣubú lulẹ̀, tí kò sì tètè rí ìtọ́jú tó fi gba ibẹ̀ jáde láyé.
Ọkùnrin kan ṣekúpa èèyàn mẹ́ta nínú ìdílé kan náà, ariwo sọ
Àwọn kan ń sọ pé ọkùnrin tó ṣá àwọn èèyàn náà ní àìsàn ọpọlọ ń dà láàmú ṣùgbọ́n BBC New Yoruba kò le fìdí èyí múlẹ̀.
Ṣé lóòótọ́ làwọn ọmọ ogun máa ń ra aṣọ ogun àti ohun ààbò fúnra wọn?- iléeṣẹ́ ológun sọ̀rọ̀
Àtẹ̀jáde kan tí adelé adarí ẹ̀ka tó ń rí sí ọ̀rọ̀ aráàlú ní iléeṣẹ́ ológun Nàìjíríà, Appolonia Anele fi léde lọ́jọ́ Ìṣẹ́gun sọ pé irọ́ tó jìnà sí òótọ́ ni ẹ̀sùn náà àti pé ó le ṣi ọ̀pọ̀ èèyàn lọ́kàn.
Wáyà iná ẹ̀lẹ́ńtíríkì já, iná ṣẹ́yọ, ṣekúpa èèyàn kan ní Ilọrin, ọ̀pọ̀ farapa, dúkìá olówó iyebíye jó mọ́lé
Àwọn èèyàn agbègbè náà ní ibi tí wọ́n ti ń gbìyànjú láti yọ ohun èlò kúrò lára iná ló ti gbé e.
Mi ò bá Makinde àti Olubadan jà, ìdí rèé táwọn èèyàn kò fi rí mi pọ̀ mọ́ Gómìnà àti Ọba Ladoja - Alaafin
Alaafin ni oun ni ibaṣepọ to dan mọran pẹlu Ọba Rashidi Ladoja ati Gomina ipinlẹ Oyo.
Wo àwọn ojú pópó tí yóò wà ní títì pa nílùú Eko lásìkò àbẹ̀wò Tinubu bẹ̀rẹ̀ láti òní
Kọmiṣọna fun igbokegbodo ọkọ nipinlẹ Eko, Oluwaseun Osiyemi, sọ ninu atẹjade kan to fi sita pe igbesẹ yii waye lati le jẹ ki eto ifilọlẹ awọn akanṣẹ iṣẹ ti Gomina Babajide Sanwo-Olu ti aarẹ fẹ ṣe lọ ni irọwọ rọsẹ.
Àwọn afurasí darandaran ṣá àgbẹ̀ sínú oko rẹ̀ l'Ogbomoso lẹ́yìn tó ní wọn kò gbọdọ̀ da ẹran níbẹ̀
Awọn afurasi darandaran naa ni wọn fẹ fi awọn maalu wọn jẹ oko oloogbe Kehinde lọjọ Isinmi, ọjọ karun un, oṣu Kẹrin ọdun 2026 yii, amọ o kọ jale ki wọn to gbẹmi rẹ.










































































