BBC News, Yorùbá - Ìròyìn
Ìròyìn tó ṣe kókó
Fídíò, "Ìdájọ́ ikú tí wọ́n dá fún àwọn tó kọlu ṣọ́ọ̀ṣì Owo kò dá ọmọ mi àti àbúrò mi méjì tí wọ́n pa padà", Duration 3,05
Awọn ti wọn padanu eeyan wọn ninu ikọlu ṣọọṣi Ọwọ ba BBC Yoruba sọrọ lẹyin idajọ iku ti awọin to ṣe ikọlu naa gba.
Ìgbákejì alága ìjọba ìbílẹ̀ l'Ekiti tí ọlọ́pàá ló jí ara rẹ̀ gbé dèrò àtìmọ́lé
Ogunjọ osu karun ọdun 2026 niroyin kan jade wi pe wọn ti ji arabinrin Ogunleye, igbakeji alaga ijọba ibilẹ ilejemeje gbe lọ nipinlẹ Ekiti.
Èyí lohun táwọn agbébọn ń béèrè lọ́wọ́ ìjọba láti tú àwọn akẹ́kọ̀ọ́ tí wọ́n jí gbé l'Ogbomoso sílẹ̀
Ninu fidio kan to ṣafihan ijokoo ile igbimọ aṣofin Oyo ni adari ile ti sọ pe ijọba ko ni sanwo fawọn agbesunmọmi lati fawọn akẹkọọ atawọn olukọ ti wọn ji gbe lominira.
Orin, Kò ṣe é má gbọ̀ ọ́, Duration 0,59
Kò ṣeé má gbọ̀ọ́
Wo àwọn agbábọ́ọ̀lù méje tí yóò gbé ògo Afrika ga nínú ìdíje ife ẹ̀yẹ agbáyé ọdún 2026
Orilẹede mẹwaa ni Afrika ni yoo kopa ninu ìdíje ife ẹyẹ agbaye ọdun 2026.
Fídíò, Eku ò ké bí eku mọ́ ní Ekiti, 'èmi ló kàn' láti dá nǹkan padà bọ̀ sípò – Oluwadare Abejide, Olùdíje ADC fún ìbò gómìnà, Duration 3,52
Oludije ẹgbẹ oṣelu ADC naa ni ibo ti ko to ibo ni wọn n yi ati wi pe nigba ti araalu ba ti di ibo wọn lọpọ yanturu, ko si bi awọn kọlọrọsin oloṣelu kankan yoo ṣe lanfani lati yii da sigbo.
Mo máa dárúkọ àwọn olóṣèlú tó ṣagbátẹrù ìjinigbé àwọn akẹ́kọ̀ọ́ l'Ogbomoso tí wọn kò bá jáwọ́ - Igboho
Igboho sọrọ yii lasiko ti ẹgbẹ awọn akẹkọọ NANS ti Akinteye Babatunde ko sodi ṣabẹwo si i nile rẹ lagbegbe Soka niluu Ibadan.
INEC àti DSS bẹ̀rẹ̀ ìwádìí lẹ́yìn tí àlàyé nípa olùdìbò lu síta lórí ayélujára
Ninu atẹjade kan lọjọ Iṣẹgun, INEC sọ pe oun gbe igbesẹ yii lẹyin ti iroyin nipa oloṣelu kan to tun jẹ gbajugbaja oṣere tiata, Emeke Ike, lu sita loju opo Continuous Voter Registration (CVR) ajọ naa.
Saheed Osupa, gbajúmọ̀ akọrin fuji ti pariwo síta lórí àwọn akẹ́kọ̀ọ́ tí wọ́n jí gbé l'Ogbomoso; ohun tó sọ rèé
Lọjọ kẹẹdogun oṣu Karun un to kọja lawọn janduku agbebọn yabo ile ẹkọ girama Esinele ati ile ẹkọ alakọbẹrẹ ijọ Onitẹbọmi Baptist Nursery and Primary School ni Yawota nibi ti wọn ti ji eeyan to le logoji gbe.
Yinka Alaseyori ṣàlàyé ara rẹ̀ lórí fídíò tó ṣe nípa àwọn akẹ́kọ̀ọ́ àtàwọn olùkọ́ tí wọ́n jí gbé l'Ogbomoso
Ṣaaju ni Yinka ti sọ ninu fidio kan to gbe jade wi pe kawọn ọmọ Naijiria tẹsiwaju lati maa gbadura lori eto aabo to mẹhẹ.
Agbébọn jí àbúrò mínísítà fún ohun àmúṣagbára tẹ́lẹ̀, Adebayo Adelabu àti ìbejì rẹ̀ gbé lọ ní Ibadan: ohun tí a mọ̀ rèé
A gbọ pe akoko ti Olaide Busayo Adegoke John-Paul atawọn ibeji rẹ, Peter ati Paul nlọ si ile ẹkọ wọn ni isẹlẹ ijinigbe ọhun waye.
Ilé ẹjọ́ dájọ́ ikú fún mẹ́rin nínú afurasí márùn ún fún ìkọlù ìjọ Kátólíkì nílùú Owo, tí wọ́n ti pa èèyàn 41 lọ́dún 2022
Ikọlu naa to waye ni ọjọ karun un oṣu kẹfa ọdun 2022 ninu eyi ti olujọsin mọkanlelogoji ti jade laye ti ogoje miran si farapa.
BBC News Yorùbá ti wà lórí ìkànnì WhatsApp
Má jẹ́ kí etí rẹ ó di sí gbogbo ìròyìn ohun tó ń lọ ní Naijiria àti káàkiri àgbáyé. Mọ̀ nípa wọn lórí ìkànnì Whatsapp rẹ
Ìròyìn Àkàgbádùn
Mo kọ N500m tí wọ́n fi lọ̀ mi láti dènà Ajimobi nígbà tó fẹ́ di gómìnà, àmọ́ ó padà gbàgbé mi- Taiwo Otegbeye
Taiwo Otegbeye lo dupo gomina ninu ẹgbẹ oṣelu Action Alliance, ni 2011.
Àwọn ilé ẹ̀kọ́ tilẹ̀kùn wọn pa l'Osun nítorí ìròyìn pé agbébọn wọ ìlú, Adeleke ní kò sí ohun tó jọ bẹ́ẹ̀
Adeleke ni awọn ọta ilu atawọn ọmọ ẹgbẹ alatako lo n gbe iroyin ẹlẹjẹ naa iri.
Ìjàmbá ọkọ̀ ló fa ikú òṣèré tíátà, 'Janmole' - Mr Latin
Aarẹ ẹgbẹ awọn oṣere TAMPAN, Ọgbẹni Bolaji Amusan, tawọn eeyan mọ si Mr Latin lo fi iroyin iku naa lede loju opo Instagram rẹ.
Èyí làwọn olóṣèlú tó fẹ́ dupò ààrẹ ní 2027 tórúkọ wọn gbilẹ̀ jù
Awọn ẹgbẹ alatako torukọ wọn gbilẹ ju ni ADC, NDC ati PDP
Àwọn orílẹ̀èdè Áfríkà wo ló jẹ àjọ IMF lówó jùlọ ?
Bi o tilẹ jẹ pe awọn orilẹede maa n lo owooya lati ajọ IMF lati fi ṣe eto ọrọ aje wọn, ẹru wiwo gbese ọlọjọ gbọọrọ lee bẹgidina idagbasoke.
Kókó ohun tó jẹyọ lásìkò àbẹ̀wò ìgbìmọ ìjọba àpapọ̀ sí Ogbomoso lórí àwọn akẹ́kọ̀ọ́ àtàwọn olùkọ́ tí wọ́n jí gbé
Igbimọ naa kọminu lori iṣẹlẹ ọhun, wọn si ṣeleri pe Aarẹ Bola Tinubu yoo sa gbogbo agbara rẹ lati doola gbogbo awọn ti wọn ji gbe.
Makinde ṣàbẹ̀wò sẹ́bí àwọn èèyàn tí wọ́n jí gbé l'Ogbomoso, ọkọ Ọ̀gá ilé ẹ̀kọ́ tí wọ́n gbé bú sẹ́kún
Makinde sọ fún gbogbo eeyan to wa nibi ipade naa to waye ni Esinele pe kí wọn ma foya torí ìjọba n ṣiṣẹ takun takun lati ri pe won doola awon t'awọn jàndùkú agbébọn ji gbe lọ.
Ẹgbẹ́ olùkọ́ bẹ̀rẹ̀ ìyanṣẹ́lódì l'Oyo lórí àwọn tí wọ́n jí gbé l'Ogbomoso, Tinubu kéde ìgbésẹ láti gba aṣógbó 1,000 síṣẹ́
Ṣaaju ni ẹgbẹ NUT ti sọ fawọn ọmọ ẹgbẹ naa nipinlẹ Oyo wi pe ki wọn ṣe ifẹhonuhan lati beere fun itusilẹ awọn tawọn janduku agbebọn ji gbe.
Seyi Makinde ni yóò ṣojú wa nínú ètò ìdìbò Ààrẹ ọdún 2027 – Ẹgbẹ́ òṣèlú APM
Ikede yii lo waye nibi eto idibo abẹlẹ ẹgbẹ oṣelu naa to waye ninu gbangan ọmọwe agba Theofilus Ogunlesi to wa ni adojuko ile iwosan UCH, nilu uIbadan.
Ẹgbẹ́ àwọn gómìnà bẹ̀rẹ̀ ìgbésẹ̀ láti máa san ₦100,000 gẹ́gẹ́ bíi owó oṣù òṣìṣẹ́ tó kéré jùlọ
Wọn ni eyii jẹ ọkan lara awọn ọna lati mu aye dẹrun fun awọn oṣiṣẹ naa latari bi ọrọ aje Naijiria ṣe le koko lonii.
Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ akẹ́kọ̀ọ́ mẹ́jọ lórí ẹ̀sùn pé wọ́n dáná sun ilé ẹkọ̀ tí akẹgbẹ́ wọn 16 ti kú
Lẹyin ti agbofinro fi ọrọ wa awọn olukọ ati ọpọ akẹkọọ lẹnuwo, ti wọn si wo ẹrọ CCTV to wa nibẹ ni wọn fidi rẹ mulẹ pe akẹkọọ mẹjọ kan lo pilẹ iṣẹlẹ naa ti wọn si sọ ina sile ẹkọ ọhun.
''Tí ìjọba bá lè gba ọmọ Yoruba láyè láti lo ìlànà ti ìbílẹ̀, ilẹ̀ wa yóò bọ́ lọ́wọ́ agbéṣùnmọ̀mí''
Ninu ọrọ rẹ pẹlu BBC Yoruba, Obarisa Ilorin Afonja, Oba Omobolaji Adifakawo Agbomola, sọ pe awọn agbara ti Afọnja fi jagun si wa sibẹ, awọn si le lo o lati sẹgun ijinigbe ati ipaniyan ti ijọba ba gba awọn laye.
Ìròyìn Pàtàkì
Kọ́milẹ́kọ̀ọ́
Ẹ tẹ̀lé wa lórí ìkànnì ayélujára
Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn
Ilé ìgbìmọ̀ àṣofin Ghana buwọ́lu òfin tó kéde ẹ̀wọ̀n ọdún mẹ́ta fún ìbálòpọ̀ akọsákọ àti abosábo
Ofin tuntun ọhun tun ke pe araalu lati fi to ijọba leti ti wọn ba kofiri ẹnikẹni to ba n ṣe nnkan naa ti wọn ti fofin de.
Àgbà òṣèré tíátà, Feso Oyewole jáde láyé
Awọn mọlẹbi oloogbe naa lo kede iroyin iku rẹ ninu atẹjade kan lọjọ Abamẹta.
Àlàyé rèé lórí bí fọ́nrán ohùn Tinubu tí wọ́n fi AI ṣe, ṣe dá wàhálà sí VDM lọ́rùn, tí wọn ṣí ló gbọdọ̀ fojú winá òfin
Bi AI ṣe wulo lati mu iṣẹ ya kankan, bẹẹ naa ni awọn to mọ lilo rẹ nidakeji tun maa n lo o lati ya fidio eeyan tabi lo ohùn ẹnu ẹni ti wọn ba fẹ fi ṣe jamba fun.
Wo kókó ohun mọ́kànlá tí Tinubu fi ránṣẹ́ sọ́mọ Náíjíríà lórí ààbò àti ọrọ̀ ajé láti sàmì ọdún kẹta rẹ̀ nípò ààrẹ
Aarẹ Bola Tinubu ni yiyọ owo iranwọ ori epo, riro owo naira lagbara lọja agbaye ati gbigbe ogun ti aabo to mẹhẹ ti oun dawọle, ti so eso rere.
Àlàyé rèé nípa fọ́tò tó ṣàfihàn Ààrẹ Tinubu tó kúnlẹ̀ níta gbangba, tí pásítọ̀ gbọ́wọ́ lé e lórí
Ninu ọsẹ yii naa ni ọrọ fọnran ohun ti wọn fi AI gbe jade bọ sori ayelujara, nibi ti wọn ti fi ohùn ẹnu Tinubu sọ awọn ọrọ to n tako araalu, to si le da rugudu silẹ.
Ọlọ́pàá méjì kú ní ìpínlẹ̀ Osun lẹ́yìn tí ọkọ̀ gbá wọn lójú pópó
Ọlọpaa orukọ awọn ọlọpaa meji ti ọrọ naa kan lede gẹgẹ bii Kehinde ati Tobi lai mẹnuba orukọ wọn keji.








































































