BBC News, Yorùbá - Ìròyìn
Ìròyìn tó ṣe kókó
Kí ni ipa tí ìdásílẹ̀ ibùdó ológun tuntun ní Omu-Aran, Kwara, yóò ní lórí àwọn ajínigbé, àgbésùnmọ̀mí àti aráàlú? Àwọn onímọ̀ sọ̀rọ̀
Atẹjade kan ti Gomina ipinlẹ Kwara, Abdulrahman Abdulrasaq fi soju opo X rẹ lọjọ Iṣẹgun, ọjọ Kọkanlelogun, oṣu Keje sọ pe ilu Omu-Aran ni ijọba ibilẹ Irepodun ni ibudo ọmọ ogun naa maa wa.
Ọkùnrin tó gbé aláìsàn wá sílé ìwòsàn Adeoyo n'Ibadan yarí pé kò sí dókítà lẹ́nu iṣẹ́, ó yájú sí Nọ́ọ̀sì, ẹgbẹ́ àwọn Nọ́ọ̀sì fọnmú
Loju ẹsẹ ti wọn sọ fun ọkunrin naa pe ko si dokita lẹnu iṣẹ ni alẹ ọjọ naa, lo ti sọ ọrọ ọhun di ariwo, to si bẹrẹ sii ṣe ikọlu si nọọsi to ba lẹnu iṣẹ.
Wo ohun tó ń fà àìsàn rọpárọsẹ̀, ìtọ́jú àti ìdènà rẹ̀, báwọn èèyàn ṣe ń ní àìsàn náà láàrin ìṣẹ́jú kọ̀ọ̀kan ní Naijiria
Lónìí àyájọ́ ìlera ọpọlọ, BBC News Yorùbá bá dókítà oníṣègùn òyìnbó sọ̀rọ̀ láti mọ ohun tó ń fa àìsàn rọlápá-rọlẹ́sẹ̀ tí a mọ̀ sí Stroke, àwọn àmì rẹ̀, ìtọ́jú àti ìdènà rẹ̀.
Fídíò, Mo gun alùpùpù fún ọjọ́ mẹ́ẹ̀dọ́gbọ̀n láti London dé Nàíjíríà láti kówójọ fún ìgbógunti àìsàn Polio - Okedeyi, Duration 4,37
BBC News Yoruba ba Olatunji sọrọ nipa ohun to mu ko gunlẹ igbesẹ gigun alupupu lati London wa si Naijiria àti awọn ipenija to koju rẹ loju ọna.
Wo gbogbo ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa WAFCON 2026
WAFCON ọdun yii yoo bẹrẹ lọjọ Aiku, ọjọ kẹrindinlọgbọn oṣu Keje ọdun 2026.
Ọlọ́pàá mẹ́rin tó gbégi dínà lójú pópó fi tipá gba rìbá N57,000 lọ́wọ́ ọ̀gá àjọ tó ń gbógun tìwà àjẹbánu, ICPC, ọ̀rọ̀ bẹ́yìn yọ
Lasiko yii, alaga ajọ to n gbogun ti iwa jibiti ati ajẹbanu nilẹ Naijiria, ICPC, Musa Aliyu ni awọn ọlọpaa kan fọwọ ṣikun ofin gbe nilu Abuja, ti wọn si fi ẹsun titapa si ofin kan an, leyi to jẹ ki wọn beere owo lọwọ rẹ.
CBN kéde ẹni tó pàṣẹ pé kí wọn ṣí àkáǹtì fún ayédèrú iléeṣẹ́ PFIPC lábẹ́ Adeniyi Adeyemi, bí Gbajabiamila ṣe ń rojọ́ níwájú àjọ ICPC
Femi Gbajabiamila farahan niwaju ajọ ICPC lẹyin ti Aarẹ Bola Tinubu paṣẹ pe ki ajọ naa ṣe iwadii finifini lori ọrọ naa.
Oluwo dá ẹgbẹ́ lọ́balọ́ba lẹ́kùn ìdìbò Ìwọ̀ oòrùn Osun sílẹ̀, di alága láéláé, àwọn ọba míì fi èrò wọn hàn
Oluwo ni awọn ọba to wa ni ẹkun iwọ oorun Osun ni wọn woye pe o yẹ ki iṣọkan wa laaarin gbogbo wọn, ti wọn si da labaa lati da igbimọ naa silẹ.
Orin, Kò ṣe é má gbọ̀ ọ́, Duration 1,02
Àkójọpọ̀ ìròyìn káàkiri àgbáyé tí kò ṣe è má gbọ̀ ọ́
Wo àwọn nǹkan mẹ́fà tó ti yípadà lẹ́yìn ìdìbò 2023 tó le nípa lórí ìdìbò 2027
Ọdun mẹrin mii tun ti de tawọn eeyan yoo tun maa dibo pẹlu gbogbo ayipada to ti waye lẹka oṣelu ati eto ọrọ aje Naijiria. Awọn ofin eto idibo ti yipada, ẹgbẹ oṣelu to n ṣe ijọba lọwọ ti mu alekun bai bi ti ọwọja wọn de tẹlẹ, tawọn oludibo naa si n koju ipenija ọtun paapaa lori igbeaye, aisi aabo ati ina ọba ti ko duro ire.
Báyìí ni ikọ̀ aláàbò Iru Ekùn ṣe ń mu àdínkù ba ìjínigbé àti ètò ààbò tó mẹ́hẹ nílẹ̀ Yorùbá pẹ̀lú ọmọ ẹgbẹ́ tó lé ní 80,000 - Sunday Igboho
Igboho lo sọrọ yii ninu atẹjade to fi sita lọjọ Aje, ọsẹ yii, to si ni ipa rere ni ileeṣẹ eleto aabo naa ti ko niu idagbasoke eto aabo lẹkun Iwọ Oorun.
Fídíò, Igun méjì ẹgbẹ́ awakọ̀ èrò dá rògbòdìyàn sílẹ̀ l'Osogbo, ìbọn ń dún lákọlákọ, aráàlú ń sá kiri, Duration 5,06
Rogbodiyan naa ti ileeṣẹ ọlọpaa Osun pada yanju, ti wọn si kilọ fawọn to da a silẹ ni wọn lo da omi alaafia ilu Osogbo, nipinlẹ Osun ru lasiko to ṣẹlẹ, to si di lilọ bibọ ọkọ lọwọ.
BBC News Yorùbá ti wà lórí ìkànnì WhatsApp
Má jẹ́ kí etí rẹ ó di sí gbogbo ìròyìn ohun tó ń lọ ní Naijiria àti káàkiri àgbáyé. Mọ̀ nípa wọn lórí ìkànnì Whatsapp rẹ
Ìròyìn Àkàgbádùn
Àwọn oníjìbìtì orí ayélujára tọwọ́ bọ ojú òpó Ààrẹ Kenya, wọ́n ń bèèrè $320,000
Lasiko ti a n kọ iroyin yii, ko ti I sẹni to mọ awọn onijibiti ori ayelujara to ṣiṣẹ naa.
Afurasí tíṣà tí wọ́n ló lu akẹ́kọ̀ọ́ pa jọ̀wọ́ ara rẹ̀ fún ọlọ̀pàá
Iṣẹlẹ naa waye niluu Adazi- Ani, nijọba ibilẹ Anaocha, ipinlẹ Anambra.
Àṣìta ìbọn agbésùnmọ̀mí pa àwọn akẹ́kọ̀ọ́ lásìkò táwọn ológun ń dènà ìjínigbé
Aṣita ibọn pa awọn akẹkọọ naa nigba ti awọn agbesunmọmi kọlu ile ẹkọ wọn lọjọ Aiku, ọjọ kọkandinlogun oṣu Keje ọdun 2026 yii.
Àdó olóró Iran ṣekúpa ọmọ ogún Amẹ́ríkà méjì, ìkọlù bẹ̀rẹ̀ lákọ̀tun
Ileeṣẹ aabo Amẹrika, US Central Command, Centcom sọ pe awọn ọmọ ogun Amerika ṣekọlu sawọn ileeṣẹ Ologun naa, ti ileeṣẹ iroyin Iran naa si fidi rẹ mulẹ pe Amẹrika ṣekọlu si Qeshm Island to wa ni odo Strait of Hormuz.
Ẹgbẹ́ àwọn Kristẹni tako òfin tó sọ ọ́ di èèwọ̀ láti máa wàásù nínú ọkọ̀ akérò
Ofin naa ni ẹnikẹni to ba jẹbi ṣiṣẹ bẹẹ yoo san ẹgbẹrun lọna aadọta naira gẹgẹ bii owo itanran tabi ko fi ẹwọn jura.
Ìdí rèé tí ìgbéyàwó èmi àti Ayinla Kollington ṣe forí ṣánpọ́n - Salawa Abeni ṣàlàyé
Lẹyin ọdun kan o le diẹ ti Kolington to sọrọ naa ni Salawa to fi ọrọ rẹ tirẹ lede ninu ifọrrọwerọ kan pẹlu Oyinmomo TV.
Ajínigbé yọ̀ǹda òkú ìyá, dẹ́rẹ́bà àti ọ̀kan lára ọmọ ìyá mẹ́ta tí wọ́n jí gbé, bèèrè N30m
Saaju ni a ti fi to yin leti pe awọn ajinigbe gbe awọn eeyan naa lasiko ti wọn n rin irinajo lati Abuja si Okelenyi, ipinlẹ Benue lati sin oku iya wọn.
Mọ̀ nípa ìtàn ife ẹ̀yẹ àgbáyé àti òdiwọ̀n góòlù tí wọ́n fi ṣe ife ẹyẹ ọdún 2026
Akọsilẹ fi han pe o to $713,000 (£532,000)
Wo ìdí tí ECOWAS ṣe fòǹtẹ̀ lu ríri ọ̀pá gáàsì láti Nàìjíríà lọ Morocco dé Yúróòpù, àti ìpè láti kọjú oro sí South Africa lórí àtakò rẹ̀ sáwọn adúláwọ̀ míì
Aarẹ Naijiria, Bola Tinubu sọ pe ti awọn olori orilẹ ede Africa ba kọ lati dakẹ, ti wọn ko ba gbiyanju pana aawọ, o ṣeeṣe ko mu alekun ba aisi igbọra ẹni ye nilẹ Africa.
Wo ẹ̀sùn mẹ́wàá tí wọ́n fi kan àwọn afurasí tó jí àwọn akẹ́kọ̀ọ́ àti olùkọ́ gbé l'Ogbomoso
Bi wọn ṣe fi Abdulrazak Umar ti inagijẹ rẹ n jẹ Abu Khalifa/Abu Khalid) han ni wọn gbe Yunusa Musa ati Shamsu Adamu ti wọn tun n pe ni Abu Itisar wa sile ẹjọ naa lati sọ ti ẹnu wọn.
Lẹ́yìn ìjà tó mú ẹ̀mí èèyàn méjì lọ l'Ojoo, ìjọba Oyo wó àwọn ilé pákó ibẹ̀
Igbesẹ naa n waye lẹyin rogbodiyan to waye lagbegbe naa laipẹ yii, eyi to gba ẹmi eeyan meji o kere tan.
Ta ni Andy Burnham tó fẹ́ di Olóòtú Ìjọba Ilẹ̀ Gẹ́ẹ̀sì tuntun?
Andy Burnham jẹ oloṣelu to ko awọn eeyan mọra, o si jẹ alaṣeyọri oloṣelu fun ọpọlọpọ ọdun ni Ilẹ Gẹeṣi.
Ìròyìn Pàtàkì
Kọ́milẹ́kọ̀ọ́
Ẹ tẹ̀lé wa lórí ìkànnì ayélujára
Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn
Ilé aṣòfin Amẹrika buwọ́lù àbá láti dá ìrànwọ́ Amẹrika fún Naijiria dúró títí tíjọba yóò fi wá ojútùú sí ìṣekúpani àwọn Kristẹni
Aṣofin Gregory Stuebe to n ṣoju ẹkun Florida lo da aba naa l'Ọjọru ki gbogbo ile to gba a wọle.
Wo bí 'Muhammad' ṣe di orúkọ tí wọ́n ń sọ ọmọkùnrin jùlọ ní England àti Wales
Abọ iwadii ti ajọ to n ri si onka ni UK iyẹn UK Statistics Office lo fidi eyi mulẹ ninu iwadii kan ti won ṣe nipa orukọ tawọn obi fun ọmọ wọn julọ lọdun to kọja.
Aisha Achimugu, bọ̀rọ̀kìnní obìnrin tí iléẹjọ́ gbẹ́sẹ̀lé ẹ̀ṣọ́ ara àti ọkọ̀ ayọ́kẹ́lẹ́ tí owó rẹ̀ tó ₦8.9bn lẹ́yìn tí EFCC fí ẹ̀sùn kíkọ́rọ̀ jọ lọ́nà èrú kàn án
Ajọ to n gbogun ti ṣiṣe owo ilu mọkumọku nilẹ Naijiria, EFCC wọn fidi iroyin naa mulẹ f'awọn akọroyin lẹyin ti idajọ naa waye lori ẹsun iwa jibiti ti wọn fi kan an.
Ohun tí a mọ̀ rèé nípa ọkọ̀ bọ́ọ̀sì tó ṣekúpa akẹ́kọ̀ọ́ ogún
Awọn alakoso orileede Uganda sọ pe yatọ si awọn akẹkọọ ogun ti wọn ba ijamba naa lọ, agbalagba kan ku, bẹẹ ni awọn miran tun farapa yannayanna ni agbegbe Kapchorwa.
Ohun tí a mọ̀ nípa ikú ọ̀dọ́bìnrin Mary Habila, òṣíṣẹ́ Mínísítà David Umahi tí wọ́n ló kú sílé rẹ̀
Iroyin sọ pe Mary, ọmọ bibi ipinlẹ Kaduna, ku lọjọ kẹtadinlọgbọn oṣu Kẹfa ọdun 2026, nile David Umahi, nigba to de si Ebonyi lẹyin irinajo ti oun ati ikọ olutọju minisita naa jọ rin.
Wo àwọn nǹkan tí o kò kà kún tó lè dí ojú òpó Wi-Fi rẹ lọ́wọ́ àti ọ̀nà àbáyọ
Oju opo Wi-Fi yii ni ohun to n so eeyan pọ mọ itakun agbaye, to n mu ayelujara si gbogbo ibi ti eeyan ba ran an lọ.
Òjò yóò rọ̀ fún ọjọ́ mẹ́wàá gbáko – Àyẹ̀wò ojú ọjọ́
Omiyale tete maa n waye nipinlẹ Eko latari bo ṣe sunmọ eti omi, paapaa alagbalugbu omi okun Atlantic Ocean.
Wo àwọn orílẹ́-èdè ilẹ̀ Afirika táwọn ọmọ ilẹ̀ Amẹrika kò gbọdọ̀ lọ
Amẹrika sọ pe ipele kẹrin ni awọn orileede mẹtalelogun ọhun wa ninu awọn orileede ti Amẹrika sọ pe awọn araalu ko gbọdọ lọ, fun idi eyi, wọn ni ko si idi pataki ti kan ti awọn eeyan fi gbọdọ lọ sibẹ.
Ohun tí a mọ̀ nípa bí Boko Haram àti ISWAP ṣe ń lo ìmọ̀ ẹ̀rọ AI fún ìgbésùnmọ̀mí
Iwadii ti fi han pe awọn Boko Haram ati ISWAP ti n lo AI, imọ ẹrọ to fẹrẹ ma si ohun ti ko le ṣe bi eeyan ba bẹ ẹ lọwẹ.











































































