BBC News,
Yorùbá
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀
Ìròyìn
Wò
Gbọ́
Àwọn abala
Ìròyìn
Idibo Naijiria 2027
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Idibo Naijiria 2027
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Coronavirus: Báyìí ni nkan ṣe n lọ ní pápákọ̀ ọkọ̀ òfurufú l'Eko lẹ́yìn tí Coronavirus wọ́lé
Àkọlé àwòrán,
Gbogbo awọn to n wọle, tabi jade kuro ni papakọ ofurufu Murtala Muhammed lo n gba abẹ ayẹwo kọja
Published
29 Èrèlè 2020
Àkọlé àwòrán,
Yatọ si irinṣẹ ti wọn n mu dani, ẹrọ kan tun wa bi kamẹra to n ṣe ayẹwo awọn eero baalu fun apẹẹrẹ aarun Coronavirus
Àkọlé àwòrán,
Oriṣiriṣi awọn oṣiṣẹ eto ilera lo wa ni ikalẹ ni papakọ ofurufu ilu Eko fun ayẹwo awọn arinrinajo
Àkọlé àwòrán,
Koda, wọn gbe omi aporo kokoro aifojuri 'sanitizer' silẹ fun awọn arinrinajo
Àkọlé àwòrán,
Ati oṣiṣẹ ati eero baalu lo n lo iboju lati ba ara wọn sọrọ nitori Coronavirus
Àkọlé àwòrán,
Kii ṣe ita papakọ ofurufu nikan ni ikiyesara ti n waye, gbagbaagba ni kaluku n boju-bomu ninu ọfiisi.
Àkọlé àwòrán,
Ẹrọ ayaworan wa tun gbe oṣiṣẹ eto ilera kan to wa lẹnu iṣẹ t'oun ti iboju ati ìbọ̀wọ́
Àkọlé àwòrán,
Ṣugbọn o, Coronavirus ko da wiwọle ati jijade ni Naijiria duro ni papakọ ofurufu naa. Kẹti-kẹti ni eero n ya lati wọ baalu.
Àkọlé àwòrán,
Igbesẹ oju lalakan fi n sọri ọhun ko yọ awọn oṣiṣẹ ajọ to n risi iwọle-wọde (Immigration) silẹ. Iboju lawọn naa fi ṣe koju o ma ri ibi.
Skip Móríwú and continue reading
Móríwú
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ
01:23
Fídíò,
Ìdí tí wíwọ ṣòkòtò àwọ̀tẹ́lẹ̀ péńpé 'boxer' sún kò fi dára tó fún ọ
, Duration1,23
05:31
Fídíò,
Ìbọn tí wọ́n yìn sí ọkọ mi kò ràn án, ìgbà tí wọ́n gba àpò ọwọ́ rẹ̀ ni ìbọn tó ràn án – ìyàwó ọmọ ẹgbẹ́ Accord tí wọ́n pa l'Esa Oke ṣalàyé
, Duration5,31
04:07
Fídíò,
Ìkà kọ́ lọmọ ejò, àwa èèyàn là ń kó tiwa bá wọn- Taiwo Okikiola-Ọmọ elejo
, Duration4,07
00:51
Fídíò,
Àǹfààní márùn-ún tó wà nínú kí obìnrin sùn láì wọ pátá
, Duration0,51
03:45
Fídíò,
N kò le fẹ́ ọkùnrin tó lówó, n kò sì le bá ọkùnrin jìyà tàbí ṣe ìyàwó kejì àbí ìkẹta - Eyiyemi Afolayan
, Duration3,45
05:08
Fídíò,
Emi ni obìńrin àkọ́kọ́ tí yóò lo wáyà iná tí kò wúlò láti ṣe iṣẹ́ ọ̀nà àwòrán - Patience Adekunle
, Duration5,08
02:35
Fídíò,
"Ó ṣe ni láàánú pé gómìnà tó fi ebi pa aráàlú, tí kò ṣe dáadáa, ni wọ́n tún fi màgòmágó dá padà síjọba"
, Duration2,35
01:46
Fídíò,
Líla ọwọ́ sí àwọn ẹbí àti ọ̀rẹ́ rẹ lè jẹ́ kí ẹ̀mí ré gùn - Ìwádìí
, Duration1,46
03:29
Fídíò,
Ìjọba Aiyedatiwa fẹ́ lé wa kúrò ní Agọ Ireti, ó tún kọ̀ láti fún wa ní owó oṣù wa – Àwọn olùgbé Agọ Ireti
, Duration3,29
02:38
Fídíò,
Abula: Eré ìdárayá tiwantiwa tí wọ́n fi orúkọ àmàlà, gbẹ̀gìrì àti ewédú sọ tó ti wá ń di gbajúmọ̀ káàkiri
, Duration2,38
04:55
Fídíò,
Ẹ má sá fún ọmọ ẹlẹ́gbẹ́, ẹnikẹ́ni tó bá fẹ́ wọn yóò là – Ifatolani Ayoka, Olórí emèrè ṣàlàyé
, Duration4,55
05:47
Fídíò,
Ademola Adeleke àti APC sọ̀kò ọ̀rọ̀ sí ara wọn lẹ́yìn ìjà òṣèlú tó wáyé l'Osun
, Duration5,47
01:13
Fídíò,
Ìdí mẹ́rin tí nǹkan ọkùnrin ṣe máa ń nàró ní àárọ̀ tí wọn bá jí
, Duration1,13
End of Móríwú
Ìròyìn tó ṣe kókó
Wàhálà bẹ́ sílẹ̀ láàárín àwọn Yorùbá àti Huasa ní Ibadan, èèyàn mẹ́ta jáde láyé
ìṣẹ́jú 31 sẹ́yìn
Wo ìdí tí ICPC fi mú dókítà tó ń tọ́jú El-Rufai àti bí aya rẹ̀ ṣe ń rọ Tinubu pé kó rántí àjọṣepọ̀
wákàtí 2 sẹ́yìn
Àṣírí ti tú nípa àwọn tó wà nídìí ìjínigbé akẹ́kọ̀ọ́ àti Olùkọ́ Esinele, ìbẹ̀rù ti ń báwọn ajínígbé náà, a ti mọ àwọn ọmọ ẹgbẹ́ wọn - Ẹ̀ṣọ́ aláàbò
wákàtí 3 sẹ́yìn
Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn
Èyí lohun tí ìjọba pinnu láti ṣe lẹ́yìn tí omíyalé fojú àwọn olùgbé ìlú Eko rí màbo
2 Agẹmo 2026
Bàbá àti ọmọkùnrin rẹ̀ mẹ́ta, afurasí ajínigbé tó ń fi màálù dídà bojú kó sí gbaga Amotekun l'Ondo
1 Agẹmo 2026
Òṣèré tíátà Mount Zion, Omooba Oluwasegun Oyeyemi jáde láyé
1 Agẹmo 2026
Àwọn ológun tí wọ́n ṣẹ̀ṣẹ̀ gbà sẹ́nu iṣẹ́ yawọ ibùgbé àwọn akẹ́kọ̀ọ́ ní Osun, gba ọ̀pọ̀ fóònù, ohun ìní wọn - Iléeṣẹ́ ológun bẹ̀rẹ̀ ìwádìí
1 Agẹmo 2026
Wo òògùn mẹ́fà tó ń dìn agbára ìbálòpọ̀ kù fún ọkùnrin àmọ́ tí ọ̀pọ̀ ṣì ń lò
1 Agẹmo 2026
Ṣé lóòótọ́ ni Oriyomi Hamzat ń ṣàtìlẹ́yìn fún AMBO olùdíje APC sípò Gómìnà l'Osun? Ohun tí a mọ̀ rèé
1 Agẹmo 2026
Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ afurasí jàndúkú olóṣèlú tó yìnbọn pa Ezekiel, ọmọ ọdún mẹ́rìnlá l'Osun
1 Agẹmo 2026
WhatsApp gbé ètò tuntun jáde pẹ̀lú lílo orúkọ fáwọn oníbàárà dìpó nọ́mbà ìbáraẹnisọ̀rọ̀
1 Agẹmo 2026
"Èyi ni ohun tí Olúwa sọ fún mi nípa ìtúsílẹ̀ àwọn akẹ́kọ̀ọ́ àti àwọn olùkọ́ tí wọ́n jí gbé l'Ogbomoso" – Pásítọ̀ Adeboye
30 Òkùdu 2026
Ìròyìn tí àwọn ènìyàn fẹ́ràn jùlọ
1
Àṣírí ti tú nípa àwọn tó wà nídìí ìjínigbé akẹ́kọ̀ọ́ àti Olùkọ́ Esinele, ìbẹ̀rù ti ń báwọn ajínígbé náà, a ti mọ àwọn ọmọ ẹgbẹ́ wọn - Ẹ̀ṣọ́ aláàbò
2
"Abuja ni ọmọ mi ní òun ti ń ṣiṣẹ́, kìí ṣe oníjọ̀ngbọ̀n, àhésọ̀ ọ̀rọ̀ nípa rẹ̀ kò yé mi tí ọlọ́pàá ṣe ba irin ara ògiri àti ìlẹ̀kùn ilé jẹ́ láti fi tipá wọlé"
3
Wo ìdí tí ICPC fi mú dókítà tó ń tọ́jú El-Rufai àti bí aya rẹ̀ ṣe ń rọ Tinubu pé kó rántí àjọṣepọ̀
4
Ìjọba àpapọ̀ kéde ìpínlẹ̀ 26 tí òjò àrọ̀rọ̀dá yóò ti wáyé fún ọ̀sẹ̀ méjìlá èyí tí yóò fa ẹ̀kún omi
5
Olórí ọmogun Naijiria ṣàlàyé ibi tí iṣẹ́ dé lori ìgbìyànjú láti dóòlà àwọn akẹ́kọ̀ọ́ àti olùkọ́ tí wọ́n jí gbé l'Ogbomoso
6
Ojú mi rí màbo láti kékeré títí mo fi délé ọkọ, mo fẹ́ pa ègún, tó ja ìyá mi àti èmi rẹ́ lórí ọmọ - Iyabo Ojo
7
Ohun tí a mọ̀ rèé nípa ìjàmbá ọkọ̀ tó ṣẹlẹ̀ sí Sam Larry níbi tí ẹ̀ṣọ́ rẹ̀ Adewale ti pàdánù ẹ̀mí rẹ̀
8
Kí ni àyájọ́ 7-7 túmọ̀ sí àti itú tàwọn ọmọ ẹgbẹ́ òkùnkùn le pa láti sàmì àyájọ́ náà
9
"N25.5m, àpò ìrẹsì, epo pẹtiró àtàwọn nńkan míì ni ajínigbé gbà lọ́wọ́ wa, káwọn èèyàn wa ní Eda Oniyo tó gba ìtúsílẹ̀, Irọ́ ni, àwa ọlọ́pàá, ológun, Àmọ̀tẹ́kùn ló gbà wọ́n sílẹ̀"
10
Davido ṣàlàyé ìdí tó fi wọ aṣọ tórúkọ àwọn akẹ́kọ̀ọ́ tí wọ́n jí gbé l'Ogbomoso wà lára rẹ̀ níbí ìdíje World Cup
More:
News
•
Sport
•
Weather
•
Worklife
•
Travel
•
Future
•
Culture
•
World
•
Business
•
Technology
•
Science_and_environment
•
Entertainment_and_arts
✕